«مَنْ صَلَّى الْبَرْدَيْنِ دَخَلَ الْجَنَّةَ»
[صحيح] - [متفق عليه]
المزيــد ...
Lati ọdọ Abu Musa Al-Ash'ariy- ki Ọlọhun yọnu si i-: Dajudaju ojiṣẹ Ọlọhun- ki ikẹ Ọlọhun ati ọla Rẹ maa ba a- sọ pé:
"Ẹni ti o ba kirun tutu mejeeji o maa wọ alujanna"
O ni alaafia - Ohun ti wọ́n fi ẹnu kò lé lórí ni
Anabi- ki ikẹ Ọlọhun ati ọla Rẹ maa ba a- ṣe wa lojukokoro lori akolekan irun tutu mejeeji, awọn mejeeji ni irun Asunbaa ati irun Alaasari, o si fun wa ni iro idunnu pe ẹni ti o ba mu mejeeji wa pẹlu ẹtọ mejeeji ninu asiko ati ni janmọọn ati eyi ti o yàtọ̀ si ìyẹn, mejeeji maa jẹ okunfa wiwọ alujanna rẹ.