عَنْ جَابِرِ بْنِ عَبْدِ اللَّهِ رضي الله عنهما أَنَّ النَّبِيَّ صَلَّى اللهُ عَلَيْهِ وَسَلَّمَ قَالَ:
«أُعْطِيتُ خَمْسًا لَمْ يُعْطَهُنَّ أَحَدٌ قَبْلِي: نُصِرْتُ بِالرُّعْبِ مَسِيرَةَ شَهْرٍ، وَجُعِلَتْ لِي الأَرْضُ مَسْجِدًا وَطَهُورًا، فَأَيُّمَا رَجُلٍ مِنْ أُمَّتِي أَدْرَكَتْهُ الصَّلاَةُ فَلْيُصَلِّ، وَأُحِلَّتْ لِي المَغَانِمُ، وَلَمْ تَحِلَّ لِأَحَدٍ قَبْلِي، وَأُعْطِيتُ الشَّفَاعَةَ، وَكَانَ النَّبِيُّ يُبْعَثُ إِلَى قَوْمِهِ خَاصَّةً وَبُعِثْتُ إِلَى النَّاسِ عَامَّةً».
[صحيح] - [متفق عليه] - [صحيح البخاري: 335]
المزيــد ...
Láti ọdọ Jaabir ọmọ Abdullahi kí Ọlọhun yọnu sí awan méjèjì, dájú dájú anọbi kí ikẹ Ọlọhun àti Ọlá Rẹ má bà sọ pé:
« wan tí fún mí ni nkán márùn tí wan kọ fún ẹni kánkan síwájú mí : wan fí ọwọ àti igbakẹ kankan mú aranse ba mí
[O ni alaafia] - [Ohun ti wọ́n fi ẹnu kò lé lórí ni] - [Sọhiihu ti Bukhaariy - 335]
Anọbi kí ikẹ àti ọlá Ọlọhun máa ba fún wa miró pé dájú dájú Ọlọhun ti fún òun ni nkán márùn tí Ọlọhun kọ fún ẹnikan nínú awani anọbi síwájú rẹ:
Alakọkọ: wan ràn mise pẹlu ìbẹrù tí wan nju sínú ọkan awàn ọtá mí , kò dá kí o já sipe kí Jinan mí sí ìbi tí wan wa le gbani ni irinajo osù kàn gbáko.
Ẹlẹẹkeji: wan se ilẹlẹ ni ààyè ifori kanlẹ fún wa tí a o máa kirun níbi kí bí tí a ba wa, wan tún se ni nkán imọra pẹlu lílo iyẹpẹ nígbàtí a bà kagara láti lọ omi.
Ẹlẹkẹta: wan se ọrọ ogún lẹtọ fún wa , òun ni nkan tí awàn musulumi nri gbà ní ojú ogún pẹlu awan alaigbagbọ.
Ẹlẹkẹrin: wan fun mí ni isipẹ tí o to bi jùlọ níbi ìfun awan ènìyàn ni ìsimi níbi ìbẹrù bojo ibuduro ọjọ igbende.
Ẹlẹkaarun: wan ràn mí sí gbogbo ẹda lapapọ àti eniyan àti alujannu wan yatọ sí ti awan anọbi tí wan síwájú rẹ, wan ran wan sí awan ìjọ wan nìkan ní .