Ìtòlẹ́sẹẹsẹ àwọn hadiisi

“Sàárà kii din dúkìá kù, Ọlọhun kii le ẹrú kún pẹ̀lú amojukuro àyàfi ni iyì, ẹnikan ko nii tẹrí ba fun Ọlọhun àyàfi ki Ọlọhun gbe e ga”
عربي Èdè Gẹ̀ẹ́sì Èdè Urdu
“Ọlọhun sọ pe: Maa na owó irẹ ọmọ Anọbi Adam, Ọlọhun maa fi òmíràn rọ́pò”
عربي Èdè Gẹ̀ẹ́sì Èdè Urdu
?Wọn mọ Isilaamu pa lori nkan márùn-ún
عربي Èdè Gẹ̀ẹ́sì Èdè Urdu
“Mẹ́fà ni àwọn iṣẹ́, mẹrin si ni àwọn èèyàn, méjì maa n sọ nǹkan di dandan, ati èyí ti o ṣe pe déédéé iṣẹ ti eeyan ba ṣe naa ni ẹsan rẹ, ati eyi ti o ṣe pe iṣẹ rere kan pẹlu ẹsan mẹ́wàá ni, ati eyi ti o ṣe pe iṣẹ rere kan pẹlu ẹẹdẹgbẹrin ẹsan ni
عربي Èdè Gẹ̀ẹ́sì Èdè Urdu
emi ni Dimaam ọmọ Tha’labah, láti ìdílé Banuu Sahd ọmọ Bakr
عربي Èdè Gẹ̀ẹ́sì Èdè Urdu